December 8, 2023 wrapanigeria

Yoruba Plateau State of Nigeria Gazette

ÒFIN LÁTI FI ÀÀYÈ SÍLẸ̀ FÚN ÌDÁSÍLẸ̀ ÌGBÌMỌ̀ FÚN Ọ̀RỌ̀ ABO ÀTI ÌBÁDỌ́GBA ÀTI FÚN ÌMÚKÚRÒ OHUN YÒÓWÙ TÍ Ó NÍ Í ṢE PẸ̀LÚ ÌWÀ ÌYANISỌ́TỌ̀ ÀTI ÀWỌN Ọ̀RỌ̀ MÌÍRÀN TÍ Ó JẸ MỌ́ ỌN.

Alábápín Ọladọọdún: Orílẹ̀-Èdè Nàìjíríà Ẹgbẹ̀rún kan Náírà, Òkè-Òkun Ẹgbẹ̀rún Mẹ́wàá àti Ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ ta Náírà. Ọ̀fẹ́ ni ìfiránńṣẹ́ . Ọ̀rọ̀ tí ó ń lọ lọ́wọ́ lọ́wọ́ (àti àwọn àfikún). Ẹgbẹ̀rún kan Náírà ni ẹyọ kan: Fi ìbẹ̀wẹ̀fún ìwé ìròyìn àti àwọn àtẹ̀ jáde ìjọba mìíràn ṣọwọ́ sí Atẹ̀wé Ìjọba ní Jos. A lè ṣe èyí nípa sísan owó sí àpò àtẹ̀wé ìjọba tàbí ìbéèrè ìfìwéránńṣẹ́sí atẹ̀wé ìjọba ní Jos. A kò gba Òǹtẹ̀ ìfìwéránńṣẹ́.

Subscribe to our
Newsletter

Contact

The organisation seeks to advance and protect the rights of women as provided by national laws and policies, regional and international treaties

No 34 Ekikunam Street Beside NUJ Secretariat, Utako-Abuja, Nigeria

About Us

Media

Get Involved

CALL: +234-818-869-9961

Contact